a
Sm 110.4
;
Isa 9.7
;
El 37.25
;
Da 7.14
.
John 12:34
34
a
Nítorí náà àwọn ìjọ ènìyàn dá a lóhùn pé, “Àwa gbọ́ nínú òfin pé, Kristi wà títí láéláé: ìwọ ha ṣe wí pé,
‘A ó gbé ọmọ ènìyàn sókè? Ta ni ó ń jẹ́ ọmọ ènìyàn yìí’
?”
Copyright information for
YorBMYO